Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

Ìgbà Wo Ló Yẹ Ká Gbẹ́kẹ̀ Lé Jèhófà?

Ìgbà Wo Ló Yẹ Ká Gbẹ́kẹ̀ Lé Jèhófà?

Ásà gbẹ́kẹ̀ lé Jèhófà nígbà táwọn ọmọ ogun tó pọ̀ gan-an dojú kọ ọ́, ìyẹn sì jẹ́ kó ṣẹ́gun (2Kr 14:9-12; w21.03 5 ¶12)

Àmọ́ nígbà tó yá, Ásà wá ìrànlọ́wọ́ lọ sọ́dọ̀ àwọn ará Síríà nígbà táwọn ọmọ ogun tí kò fi bẹ́ẹ̀ pọ̀ wá gbógun jà á (2Kr 16:1-3; w21.03 5 ¶13)

Inú Jèhófà ò dùn sí Ásà torí pé kò gbẹ́kẹ̀ lé e mọ́ (2Kr 16:7-9)

A máa gbára lé Jèhófà tá a bá fẹ́ ṣe àwọn ìpinnu tó ṣe pàtàkì. Àmọ́ tá a bá fẹ́ ṣe àwọn nǹkan tí kò fi bẹ́ẹ̀ ṣe pàtàkì ńkọ́? Ó yẹ ká máa gbára lé Jèhófà nínú gbogbo ohun tá a bá ń ṣe.​—Owe 3:5, 6; w21.03 6 ¶14.